Skip to content
الإنسَان /

Ẹsẹ 12

76 : 12
الإنسَان Àwọn Ẹsẹ 31
Súrà · الإنسَان
Yorùbá · Mikail
76 : 12

وَجَزَىٰهُم بِمَا صَبَرُواْ جَنَّةٗ وَحَرِيرٗا

Ó sì máa san wọ́n ní ẹ̀san Ọgbà Ìdẹ̀ra àti aṣọ àlàárì nítorí pé wọ́n ṣe sùúrù.