Skip to content
القَلَم /

Ẹsẹ 15

68 : 15
القَلَم Àwọn Ẹsẹ 52
Súrà · القَلَم
Yorùbá · Mikail
68 : 15

إِذَا تُتۡلَىٰ عَلَيۡهِ ءَايَٰتُنَا قَالَ أَسَٰطِيرُ ٱلۡأَوَّلِينَ

nígbà tí wọ́n bá ń ké àwọn āyah Wa fún un, ó máa wí pé: “Àkọsílẹ̀ àlọ́ àwọn ẹni àkọ́kọ́ (nìwọ̀nyí)”.