Skip to content
الإنسَان /

Ẹsẹ 24

76 : 24
الإنسَان Àwọn Ẹsẹ 31
Súrà · الإنسَان
Yorùbá · Mikail
76 : 24

فَٱصۡبِرۡ لِحُكۡمِ رَبِّكَ وَلَا تُطِعۡ مِنۡهُمۡ ءَاثِمًا أَوۡ كَفُورٗا

Nítorí náà, ṣe sùúrù fún ìdájọ́ Olúwa rẹ. Má ṣe tẹ̀lé ẹlẹ́ṣẹ̀ tàbí aláìmoore kan nínú wọn.