Skip to content
مَريَم /

Ẹsẹ 36

19 : 36
مَريَم Àwọn Ẹsẹ 98
Súrà · مَريَم
Yorùbá · Mikail
19 : 36

وَإِنَّ ٱللَّهَ رَبِّي وَرَبُّكُمۡ فَٱعۡبُدُوهُۚ هَٰذَا صِرَٰطٞ مُّسۡتَقِيمٞ

Àti pé dájúdájú Allāhu ni Olúwa mi àti Olúwa yín. Nítorí náà, ẹ jọ́sìn fún Un. Èyí ni ọ̀nà tààrà.