Skip to content
البُرُوج /

Ẹsẹ 9

85 : 9
البُرُوج Àwọn Ẹsẹ 22
Súrà · البُرُوج
Yorùbá · Mikail
85 : 9

ٱلَّذِي لَهُۥ مُلۡكُ ٱلسَّمَٰوَٰتِ وَٱلۡأَرۡضِۚ وَٱللَّهُ عَلَىٰ كُلِّ شَيۡءٖ شَهِيدٌ

Ẹni tí Ó ni ìjọba àwọn sánmọ̀ àti ilẹ̀. Allāhu sì ni Ẹlẹ́rìí lórí gbogbo n̄ǹkan.